BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Kí ló fá ikú ọ̀pọ̀ èèyàn tó ń jí epo rọ̀bì fà ní Okrika, ìpínlẹ̀ Rivers? Ohun tí a mọ̀
Nnkan bi agogo mejila ori, Ọjọbọ, ọsẹ yii, ọjọ kẹta, oṣu Kẹsan, ọdun 2026 ni iṣẹlẹ naa waye ni adugbo Okari Jetty, iyẹn lagbegbe Okrika Mainland.
Báyìí ni ìgbẹ́jọ́ awakọ̀ Anthony Joshua tún ṣe lọ àti àwọn kókó ẹ̀sùn mẹ́rin tí olùpẹ́jọ́ gbé kalẹ̀
Wọn sọ fun ile ẹjọ pe niṣe ni Joshua atawọn ọrẹ rẹ ti sun lọ ninu ọko Lexus SUV ti wọn wa nigba ti wọn n lọ si ilu Sagamu ki ijamba naa to waye.
Àṣírí ibi tí wọ́n ti n ṣe ayédèrú owó Euro tú n'ibadan, àwọn afurasí há
Ẹgbẹrun mẹjọ ati ẹẹdẹgbẹrun owo Euro ti gbogbo rẹ ayederu ni ọlọpaa sọ pe awọn gba lọwọ awọn afurasi naa.
Fídíò, Bukky Wright sọ̀rọ̀ lórí ikú Kola Oyewo àti Ogogo, bí wọn kò ṣe pe ọ̀pọ̀ àgbà òṣèré tó jìyà tíátà sí iṣẹ́ mọ́ àti ohun tí ìjọba le ṣe láti ṣèrànwọ́, Duration 3,17
Bukky Wright, lásìkò tó ń bá BBC News Yorùbá sọ̀rọ̀ nípa ikú àwọn òṣèré tíátà, ṣe àgbékalẹ̀ ọ̀nà bí ìjọba ṣe le ràn wọ́n lọ́wọ́ láti pọn omi sílẹ̀ de òùngbẹ.
Àlàyé rèé lórí bí a ṣe ṣàwárí, dóòlà àwọn tí ajínigbé gbé ní Oriire, ọ̀nà táwọn èèyàn mẹ́sàn-án gbà kú àti ọ̀pọ̀ òfegè ìròyìn nípa ìṣẹ̀lẹ̀ náà - Ọ̀gá DSS
Awọn ti ko din ni mẹrindinlaadọta, olukọ meje ati akẹkọọ mọkandinlogoji ni awọn janduku agbebọn naa jigbe wọnu igbo lọ.
Sunday Igboho sọ̀rọ̀, orí ayélujára tún gbóná jain-jain, áláyé rèé
Ninu fidio kan to gba ori ayelujara ni Igboho ti n sọ fun awọn ẹṣọ aabo naa pe agbebọn ti wọn ba ti ba ibọn lọwọ rẹ ninu igbo ni ki wọn pa lẹyẹ o sọka.
Ilé aṣojú-ṣòfin rí àpò àṣùwọ̀n owó 58 tó so mọ́ Adeniyi Adeyemi, bó ṣe wẹ Gbajabiamila mọ́ pé kò mọwọ́-mẹsẹ̀ nípa ayédèru iléeṣẹ́ PFIPC
Bakan naa ni wọn fidi rẹ mulẹ pe Gbajabiamila lo n ṣiṣẹ tako idasilẹ awọn ayederu ileeṣẹ yii, ti aṣiri rẹ fi tu sita fun gbogbo araye.
Fídíò, Ṣé òótọ́ ni pé àwọn Kristẹni nìkan làwọn jàndùkú agbébọn ń kọlù ní Naijiria?, Duration 2,00
Bo tilẹ jẹ pe ijọba Naijiria n gbiyanju lati koju irufẹ ikọlu ọhun, ikọlu awọn agbebọn ti di lemọlemọ ni Naijria.
Orin, Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́, Duration 0,59
Àkójọpọ̀ ìròyìn káàkiri àgbáyé tí kò ṣe è má gbọ̀ ọ́
Kí ló dé tí ẹnu ń kun Sarafadeen Alli, olùdíje sípò gómìnà l'Oyo, torí fọ́nrán ibi tó ti gbé akẹ́kọ̀ọ́-kùnrin kan sórí ẹsẹ̀?
Ninu fọnran naa to n kaakiri ori ayelujara lati Ọjọru, ọsẹ yii, la ti ri Alli, ẹni to tun jẹ Sẹnetọ to n ṣoju ẹkun Guusu ipinlẹ Oyo lọwọ nile igbimọ aṣofin, to gbe akẹkọọ ile-ẹkọ gbogboniṣe tiluu Ibadan lori ẹsẹ, tí wọn sì ló ń fi ọwọ́ pa á lára.
'Àwọn èèyàn parọ́ mọ́ wa pé a jí nǹkan ọmọkùnrin ẹnìkan, àyélujára sì gbà bẹ́ẹ̀'
O le ni eeyan 80 ti wọn ti ku iku aitọjọ lẹyin ti wọn lu wọn pa lori ẹsun pe wọn pe wọn ji nnkan ọmọkunrin ẹlomii.
Ìdí rèé tí Uber fi kógbá wọlé ní Naijiria lẹ́yìn ọdún méjìlá tó fi ṣe okòwò ọkọ̀ èrò
Uber ṣalaye wi pe igbesẹ to nira lo jẹ fawọn lati kuro ni Naijiria, amọ, nnkan ti okowo awọn n fẹ ni awọn ṣe.
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Ta ló ń pààrọ̀ orúkọ àwọn olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú NDC lójú òpó àjọ elétò ìdìbò, bí INEC ṣe sẹ́ pé òun kọ́?
Alaga agba fun ẹgbẹ oṣelu NDC, Sẹnetọ Moses Cleopas Zuwoghe lo pariwo yii sita lọjọ Aiku ana, lẹyin ti ajọ INEC fi orukọ awọn oludije lẹgbẹ oṣelu sita.
Kí ló ṣe Adewale Eleso, gbajúmọ̀ òṣèré tíátà tó fi ṣiṣẹ́ abẹ, ipò wo sì ni ìlera rẹ̀ wà?
Atẹjade ti agbẹnusọ agba fun ẹgbẹ oṣere ANTP, Ọmọọba Adejonwo Oluwafemi fi sita loju opo Facebook rẹ ni Eleso ti ṣiṣẹ abẹ tori egbo oju rẹ naa.
Àwọn ọmọ ogun wa nílẹ̀ Áfríkà ló dìde ìrànlọ́wọ́ láti kojú ìdìtẹ̀gbàjọba tó fẹ́ẹ́ wáyé ní Niger - Russia ṣàlàyé
Niṣe ni iro ibọn n dun lakọlakọ, ti ado oloro si n dun kaakiri ni Niamey ni owurọ kutukutu ọjọ Abamẹta gẹgẹ bi awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ṣe sọ.
Ìdí rèé tí Dangote fi ṣe àfikún owó epo bẹntiróòlù fún ìgbà mẹ́ta láàrin ọ̀sẹ̀ kan àti ipa rẹ̀ lórí aráàlú
Ile ifọpo Dangote sọ pe afikun owo epo bẹntiroolu naa ko ṣẹyin epo rọbi ọwọnlọwọn ti ileeṣẹ naa ti ra lati oke okun papaa julọ lasiko ti owo epo rọbi lọ soke lọja agbaye.
Ọ̀rọ̀ oyè Awujale tún gba ọ̀nà míì yọ, bí igbákejì alága ìdílé Funsegbuwa ṣe wọ́ àwọn èèyàn tó ya kúrò nínú ìdílé lọ sílé ẹjọ́, bèèrè N10bn
Ni ọjọ Kẹrinlelogun, oṣu Kẹjọ ni Oloye Fassy wọ awọn eeyan naa lọ siwaju ile ẹjọ giga ipinlẹ Ogun fun ẹsun ibanilorukọjẹ to si n beere fun owo itanran biliọnu mẹwaa naira gẹgẹ bi owo itanran.
A ti gba mílíọ́nù márùndínlọ́gbọ̀n Náírà owó tí Ogogo gbé fún Ìmáàmù àgbà Ilaro padà - Ẹbí Ogogo
Imam agba Mustapha ló tan imole sì ọrọ naa lowuro ojo Aje níbi ayẹyẹ fidau fun Ologbe Taiwo Hassan Ogogo to waye lonii ọjọ Aje.
Ṣé lóòótọ́ ni OPay fẹ́ kógbá wọlé ní Naijiria lónìí ọjọ́ kíní oṣù Kẹ́sàn án? Ohun tí a mọ̀ rèé
Nínu atẹjade kan ti OPay fi sita loju opo ayelujara rẹ, ileeṣẹ OPay fi ọkàn awọn onibaara rẹ balẹ wi pe ki wọn ma fòyà torí ileeṣẹ naa ko lọ ibikan.
Àlàyé rèé lórí ipa táwọn ikọ̀ aláàbò kó lórí báwọn Àgùnbánirọ̀ mẹ́ẹ̀dógún, aráàlú mẹ́fa, tí wọn jí gbé ní Kogi, ṣe gba ìtúsílẹ̀ àti ohun tí ààrẹ Tinubu sọ
Kii ṣe awọn agunbanirọ yii nikan lawọn ajinigbe digun ko salọ, bi ko ṣe pe wọn tun ji awọn araalu gbe pẹlu wọn, eyi ti apapọ gbogbo wọn jẹ mọkanlelogun.
Lẹ́yìn ọgbọ̀n ọdún, ilé ẹjọ́ kéde olórí ikọ̀ gàńfé bí ẹni tó jẹ̀bi ẹ̀sùn ikú Tupac Shakur
Adajọ ni Davis jẹbi ẹsun ipaniyan pẹlu lilo ohun ija oloro nibi ti wọn ti yibọn pa Tupac ni Las Vegas lọjọ Keje, oṣu Kẹsan-an, ọdun 1996.
Àlàyé rèé lórí ohun táwọn dókìtà nílé ìwòsàn LAUTECH ń bèèrè fún, bí ìyanṣẹ́lódì wọn ṣe wọ ọjọ́ mẹ́rin
Ẹgbẹ awọn dokita ile iwosan naa sọ pe awọn ko i tii gbọ ohunkohun lati ọdọ ijọba ipinlẹ Oyo lati ọjọ Ẹti, ọjọ Kejidinlọgbọn, oṣu Kẹjọ ti wọn ti gunle iyanṣẹlodi naa.
A ti ṣetán láti ṣàtìlẹ́yìn fún ìjọba lórí ètò ààbò tó mẹ́hẹ – OPC
Ọrọ yii lo jẹyọ lọjọ Abamẹta nibi ti awọn ọmọ ẹgbẹ naa ti n ṣe iranti idasilẹ ẹgbẹ ọhun lọdun mejilelọgọbọn sẹyin.
Wo àwọn ọ̀nà tí o lè gbà láti ṣọ́ owó ná lórí oúnjẹ lásìkò ọ̀wọ́ngógó yìí
Bo tilẹ jẹ pe ọpọ eeyan lo ti n ṣe bi wọn ṣe mọ, ọpọ awọn mii lo ṣi n wa ọna lati ni owo diẹ lọwọ lẹyin ti wọn ba ra ounjẹ sile tan.
Ìròyìn Pàtàkì
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Gómìnà Adeleke, mo kí ẹ kú oríire pé o wọlé fún sáà kejì àmọ́ ọ̀rọ̀ sì kù lẹ́yìn rẹ̀ - Oyebamiji, olùdíje gómìnà APC l'Osun
Oyebamiji nigba to n ba awọn ọmọ ẹyin ati alatilẹyin rẹ sọrọ fun igba akọkọ lẹyin eto idibo naa, iyẹn lọjọ Abamẹta to kọja, lo ti sọ pe oniruuru aṣemaṣe lo waye lasiko eto idibo naa.
Wo ìdí pàtàkí mẹ́rin tí Ààrẹ Tinubu kò ṣe fẹ́ kí ilẹ̀ Amẹ́ríkà fí àkọsílẹ̀ rẹ̀ nípà egbòogi olóró síta
Ninu iwe naa ni wọn ti sọ pe ofin anfaani si iroyin ati idaabo bo ẹtọ ọmọniyan yẹ ko jọba lori ṣiṣe afihan awọn akọsilẹ wọn, ati pe ko sẹnikẹni to fẹẹ mọ nipa rẹ.
Gómìnà Adeleke gbé ìgbìmọ̀ dìde láti ṣe ìwádìí àwọn ìpànìyàn tó wáyé nílùú Ikire
Igbimọ oluwadii naa ti adajọ Majisireeti Ayokunle Shiyanbola ko sodi ni wọn yoo ṣewadii ohun to ṣokunfa ikọlu naa, ṣe agbejade iye ati orukọ awọn to fori sọta iṣẹlẹ naa, ṣewadii ohun to ikọlu ọhun ati boya o ni nnkan ṣe pẹlu iku to waye nibẹ.
Kí ló mú kí ọkùnrin kan fi ọ̀bẹ pa èèyàn kan nílé sinimá l'Eko, tí ẹ̀mí òun náà fi bọ́? Àlàyé rèé
Ọkunrin kan ti wọn lo ti fa ifakufa sara ni wọn lo gun ẹṣọ aabo ile iworan naa titi to fi jade laye, to si tun ṣe ẹṣọ aabo miran leṣe, iyẹn lalẹ ọjọ Ẹti to kọja yii.
Alága APC ìpínlẹ̀ Kogi tí agbébọn yìnbọn pa, ohun tí a mọ̀ rèé
Awọn to pa a naa ṣa deede ya jade lati inu igbo to wa nitosi, wọn si bẹrẹ si i yinbọn si awọn ọkọ to n lọ.
Wo ọ̀nà àrékérekè tuntun táwọn agbésùnmọ̀mí ń gbà r'owó ní Naijiria bàyìí yàtọ̀ sí gbígba owó ìtúsílẹ̀
ẹka kan to n ri si itọpinpin ibi towo n gba wọle, 'Nigeria Financial Intelligence Unit' (NFIU) ti sọ pe awọn agbebọn n fi ojoojumọ lekun si i nipa ọna ati maa rowo ṣiṣẹ laabi wọn ni.
Àìsàn jẹjẹrẹ kọlu àgbà òṣèrè mííràn
Dasofunjo rọ awọn ọkunrin kaakiri agbaye lati maa wa ni ikiyesara lori aisan jẹjẹrẹ to nii ṣe pẹlu nnkan ọmọkunrin, iyẹn prostrate cancer.










































































